Excellent Media Tv

Excellent Media Tv

Share

Digital content creator

09/06/2026

Ijọba Ọyọ ti wo ile ti awọn ajinigbe to ji aburo Adelabu ati awọn ibeji rẹ n lo danu

L'Ọjọ Aje, Mọnde, ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹfa, ọdun 2026 yii, ni ijọba ipinlẹ Ọyọ, lọọ wo ile ti wọn gbe àbúrò Adelabu iyẹn Ọlaide Adegoke John Paul ati ọmọ ẹ ibeji si danu, èyí tó wa lagbegbe Lakoun, Ayegun-Olojuoro niluu Ibadan.

Tẹ o ba gbagbe, lọjọru, ọṣẹ to kọja, ni wọn ji aburo minisita tẹlẹ lorileede yii, Adebayọ Adelabu, tọpọ tun mọ si Pẹnkẹlẹmẹsi, ni wọn ji aburo rẹ ati ọmọ ibeji ẹ gbe, tí wọ́n si doola wọn lọjọ Abamẹta, Satide yii.

Ilé ti wọn ti doola wọn ọhun, tí àwọn ajinigbe ń lọ ní wọn lọọ dawo lulẹ bayii.

07/06/2026

BREAKING NEWS: Ogbomoso Chief Imam Breaks Silence on Terror Links Allegation, Threatens Legal Action Against Bloggers ❤️🔥

The Grand Chief Imam of Ogbomosoland, Imam Yunus Olushina Teliat (Ayilara II), has finally broken his silence over allegations linking him to terrorism and criminal activities, describing the claims as "malicious, coordinated, and completely false."

In a strongly-worded statement released on Sunday, the respected Islamic cleric expressed deep concern over the abduction of schoolchildren and teachers in Ahoro, Esin-ele, and Yawota communities, while calling on the Federal and Oyo State Governments to intensify rescue efforts.

The cleric reaffirmed his long-standing condemnation of terrorism, kidnapping, and banditry, stressing that he has repeatedly denounced such crimes in sermons and public lectures, even advocating severe punishment for convicted perpetrators.

However, the Imam reserved some of his strongest words for individuals spreading allegations against him, warning bloggers, vloggers, and social media users to immediately stop associating his name with criminal activities.

According to him, his legal team has already commenced action against individuals behind what he described as defamatory and libelous publications, vowing to pursue further offenders through the courts.

While praying for the safe return of the abducted victims and peace across Nigeria, the Chief Imam maintained that his life's mission remains promoting justice, peace, and the protection of human lives.

Want your business to be the top-listed Media Company in Osun?
Click here to claim your Sponsored Listing.

Category

Address

Jamodo/Janta/Obada Area, Ifon Osun
Osun